Nuacht

Ní ilé ààrẹ Aso Rock tó wà ní ìlú Abuja ni ààrẹ ti gbàlejò àwọn agbábọ́ọ̀lù náà lẹ́yìn tí wọ́n padà sí Nàìjíríà láti Morocco tí ìdíje náà ti wáyé.